Shehu Sani: Buhari yẹ kó foyè dá àwọn akọni tókù lọ́lá pẹ̀lú
Oríṣun àwòrán, Sheu Sani /twitter
Senetọ Shehu Sani ti kede pe o yẹ kí ààrẹ Muhammadu Buhari bẹ idile àwọn ogoni to sọ ẹ̀mí wọn nu wò.
O mẹnuba awọn bii Ken Saro Wiwa, Sheu Musa Yaradua, Bẹẹkọ Kuti, àti Chinma Ubani nítorí àwọn náà kú fún ìjọba awa-ara-wa.
Senetọ Sheu Sani, tó n sojú ẹkùn aarin gbùngbùn Kaduna, ló kàn sí ààrẹ Buhari bẹ́ẹ̀ lórí ìkànni Twitter rẹ.
O ni pé, ìdílé Gani Fawehinmi àti MKO Abiola nìkan kọ́ lo kú fún ìjọba àwa-ara-wa, atí wipe ó pọn dandan lati bẹ ìdílé awọn akọni fun ijọba tiwantiwa yooku wo pẹ̀lú ìfàmì ẹ̀yẹ̀ dawọn lọ́lá.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
Sẹnetọ Sani pe awọn ìdílé àwọn ènìyàn wọ̀nyìí pẹ̀lú nílo ìwúrí láti ọ̀dọ̀ ìjọba.
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
Content is not available
{{rankTranslation}}