BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
COZA: Àdúrà kò le pa ìfipábánilòpọ̀ rẹ́, àtàwọn àkọlé mìí tó jẹyọ lórí ọrọ Fatoyinbo
30 Òkùdu 2019
Awọn eniyan ko ara wọn jọ lati fẹhonu han ni ẹka ijọ COZA ni ilu Abuja ati Eko.
Àkọlé àwòrán,
Ara wa kii ṣe nkan iṣere yin, a kọ ifipabanilopọ
Àkọlé àwòrán,
Tọkunrin-tobinrin lo pejọ sibi iwọde naa
Àkọlé àwòrán,
Iwọde naa fa sunkẹrẹ-fakẹrẹ ọkọ loju ọna Mobolaji Bank Anthony, Ikẹja nibi ti ijọ COZA wa l'Eko
Àkọlé àwòrán,
Obinrin yii n sọ pẹlu akọle ọwọ rẹ pe 'ẹ maa gba awọn obinrin gbọ
Àkọlé àwòrán,
'Adura ko le pa ifipabanilopọ rẹ.'
Àkọlé àwòrán,
Ẹ ma fi orukọ Ọlọrun daabo bo afipabanilopọ
Àkọlé àwòrán,
Sọrọ sita lasiko yii, ma pa ẹnu rẹ mọ ti wọn ba fi ipa ba ọ l'opọ.
Àkọlé àwòrán,
Aṣọ funfun ni awọn to fẹhonu han wọ lati polongo tako ifipabanilopọ
Àkọlé àwòrán,
Bi wọn ṣe n sọ pe Pasitọ ko ga ju ofin lọ, ni wọn pe iwọ ko gbọdọ fi ipa banilopọ.
Àkọlé àwòrán,
Fọfọ̀ ni ẹnu ọna ẹka ijọ COZA to wa ni ilu Eko kun fun awọn to n ṣewọde pe ki Pasitọ̀ Fatoyinbo fi ipo rẹ silẹ
Àkọlé àwòrán,
Ọ̀kan lara awọn akọle yii n sọ pe didaabo bo ẹni to fi ipa banilopọ kii ṣe iwa Kristi
Àkọlé àwòrán,
Pasitọ kii ṣe Ọlọrun; Ọlọrun le dariji ọ l'ẹwọn
Àwọn afíkun lórí ìròyìn yìí
Ìjọ Satani dá MI lóhùn lórí ọ̀rọ̀ Fatoyinbo
30 Òkùdu 2019
COZA: Mi ò fípá bá obìrin lò pọ̀ rí láyé mi - Pásítọ̀ Fatoyinbo
29 Òkùdu 2019